Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 28:5-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ tí ó jẹ́ ìdámẹ́wàá éfà ìyẹ̀fun dáradára tí a pò pọ̀ mọ́ ìdámẹ́rin hínì òróró tí a yọ lára Ólífì.

6. Èyí ni ẹbọ sísun gbogbo ìgbà tí a fi lẹ́lẹ̀ ní òkè Sínáì gẹ́gẹ́ bí olóòrùn dídùn ẹbọ tí a fi iná sun fún Olúwa pẹ̀lú iná.

7. Àfikún ọrẹ ohun mímu rẹ gbọdọ̀ jẹ́ ìdámẹ́rin ti hínì dídé omi mímu tí ó kan pẹ̀lú ọ̀kọ̀ọ̀kan ọ̀dọ́ àgùntàn. Da ẹbọ mímu náà síta sí Olúwa ní ibi mímọ́.

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 28