Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóòbù 1:6-9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

6. Ǹjẹ́ ó di ọjọ́ kan, nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run wá í pé níwájú Olúwa, Sàtánì sì wá pẹ̀lú wọn.

7. Olúwa sì bi Sàtanì wí pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?”Nígbà náà ní Sàtanì dá Olúwa lóhùn wí pé, “Ní ìlọ-siwá-sẹ́yìn lórí ilẹ ayé, àti ní ìrìnkèrindò nínú rẹ̀.”

8. Olúwa sì sọ fún Sàtanì pé ìwọ ha kíyèsí Jóòbù ìránṣẹ́ mi, pé kò sí èkejì rẹ̀ ní ayé, ọkùnrin tí í ṣe olóòótọ́, tí ó sì dúró ṣinṣin, ẹni tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run, ti ó sì kóríra ìwà búburú.

9. Nígbà náà ni sátanì dá Olúwa lóhùn wí pé, “Jóòbù ha bẹ̀rù Olúwa ní asán bí?

Ka pipe ipin Jóòbù 1