“Njẹ́ nítorí náà nísínsin yìí,” ni Olúwa wí,“Ẹ fi gbogbo ọkàn yín yípadà sí mi,àti pẹ̀lú ààwẹ̀, àti pẹ̀lú ẹkún, àti pẹ̀lú ọ̀fọ̀.”