Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Àìsáyà 6:11-13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

11. Nígbà náà ni mo wí pé, “Báwo ni yóò ti pẹ́ tó Olúwa?”Òun sì dáhùn pé:“Títí tí gbogbo ìlú ńlá yóò fi dahoroláìsí olùgbé nínú un rẹ̀ mọ́,títí tí gbogbo ilé yóò fi di ìkọ̀sílẹ̀tí gbogbo ilé yóò sì di àlàpà àti ahoro,

12. títí tí Olúwa yóò fi rán gbogbo wọn jìnnà rérétí ilẹ̀ náà sì di ìkọ̀sílẹ̀ pátapáta.

13. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìdámẹ́wàá ṣẹ́kù lórí ilẹ̀náà, yóò sì tún pàpà padà parunṢùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí igi tẹ́rẹ́bíńtì àti óákùti í fi kùkùté sílẹ̀ nígbà tí a bá gé wọn lulẹ̀bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni irúgbìn mímọ́ náà yóò di kùkùté níilẹ̀ náà.”

Ka pipe ipin Àìsáyà 6