Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Àìsáyà 38:1-4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ní ọjọ́ náà ni Heṣekáyà ṣe àìṣàn dé ojú ikú. Wòlíì Àìṣáyà ọmọ Ámósì sì lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé, “Ohun tí Olúwa wí nìyìí: palẹ̀ iléẹ̀ rẹ mọ́, bí ó ti yẹ nítorí pé ìwọ yóò kú; ìwọ kì yóò dìde àìṣàn yìí.”

2. Heṣekáyà yí ojúu rẹ̀ sí ara ògiri, ó sì gba àdúrà sí Olúwa,

3. “Rántí, Ìwọ Olúwa, bí mo ti rìn pẹ̀lú òtítọ́ níwájúù rẹ, àti bí mo ti fi ọkàn dídúró ṣinṣin ṣe ohun tí ó dára ní ojúù rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni Heṣekáyà sì ṣunkún kíkorò.

4. Lẹ́yìn náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Àìṣáyà wá pé

Ka pipe ipin Àìsáyà 38