Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Àìsáyà 18:5-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Nítorí, kí ìkóórè tó bẹ̀rẹ̀, nígbà tíìtànná kò sí mọ́,nígbà tí ìtànná di èso tí ó ń pọ́n bọ̀.Òun yóò sì fi ọ̀bẹ ìwẹgi gé àwọ ìsó tuntun kúrò,yóò sì gé àwọn ẹ̀ka tí ó ńgbilẹ̀ lulẹ̀ a sì kó wọn dànù.

6. Gbogbo wọn la ó fi lé àwọn jẹran jẹran ẹyẹlọ́wọ́ lórí òkèàti fún àwọn ẹranko búburú;àwọn ẹyẹ yóò fi wọ́n ṣoúnjẹ nínú ẹ̀ẹ̀rùnàti àwọn ẹranko búburú nígbà òjò.

7. Ní àkókò náà ni a ó mú ẹ̀bùn wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogunláti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn gíga tí ẹran ara wọn jọ̀lọ̀,láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tí a bẹ̀rù níbi gbogbo,orílẹ̀ èdè aláfojúdi àti alájèjì èdè,ilẹ̀ ẹni tí omi pín sí yẹ́lẹyẹ̀lẹ—a ó mú àwọn ẹ̀bùn náà wá sí òkè Síónì, ibi tí orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbé wà.

Ka pipe ipin Àìsáyà 18