Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Onídájọ́ 4:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Dèbórà sì wí fún Bárákì pé, “Lọ! Lónìí ni Olúwa fi Ṣísérà lé ọ lọ́wọ́, Olúwa ti lọ ṣíwájú rẹ.” Bárákì sì ṣíwájú, àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá sì tẹ̀le e lẹ́yìn, wọ́n sì kọjá sí òkè Tábórì.

Ka pipe ipin Onídájọ́ 4

Wo Onídájọ́ 4:14 ni o tọ