Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Dáníẹ́lì 11:40 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Ní ìgbà ìkẹyìn, ọba Gúṣù yóò gbé ogun de sí i, ọba àríwá yóò sì jáde bí ìjì láti kọ lù ú pẹ̀lú u kẹ̀kẹ́ ogun àti ẹlẹ́ṣin àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ̀ ojú omi. Yóò gbógun wọ orílẹ̀ èdè púpọ̀, yóò sì gbá wọn mọ́lẹ̀ bí ìkún omi.

Ka pipe ipin Dáníẹ́lì 11

Wo Dáníẹ́lì 11:40 ni o tọ