Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ámósì 6:3-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

3. Ẹ̀yin sún ọjọ́ ibi síwájú,ẹ sì mú ìjọba òǹrorò súnmọ́ tòòsí

4. Ẹ̀yin sùn lé ibusùn tí a fi eyín erin ṣeẸ sì tan ara sílẹ̀ ni orí àwọn ibùsùnẸ̀yin pa èyí tí o dára nínú àwọn ọ̀dọ́ àgùntàn yín jẹẸ sì ń pa àwọn ọ̀dọ́ màlúù láàrin agbo wọn jẹ

5. Ẹ̀yin ń lo ohun èlò orin bí i DáfídìẸ sì ń ṣe àwọn àpilẹ̀rọ̀ àwọn ohun èlò orin

6. Ẹ̀yín mu wáìnì ẹ̀kún ọpọ́n kanàti ìkunra tí o dára jùlọṢùgbọ́n ẹ̀yin kò káànú ilé Jósẹ́fù tí o di ahoro

Ka pipe ipin Ámósì 6