Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

1 Ọba 2:45-46 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

45. Ṣùgbọ́n a ó sì bùkún fún Sólómónì ọba, ìtẹ́ Dáfídì yóò sì wà láìfòyà níwájú Olúwa títí láéláé.”

46. Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Bénáyà ọmọ Jéhóíádà, ó sì jáde lọ, ó sì kọlu Ṣíméhì, ó sì pa á.Ìjọba náà sì wá fi ìdí múlẹ̀ ní ọwọ́ Sólómónì.

Ka pipe ipin 1 Ọba 2