Àìsáyà 18:5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
Nítorí, kí ìkóórè tó bẹ̀rẹ̀, nígbà tíìtànná kò sí mọ́,nígbà tí ìtànná di èso tí ó ń pọ́n bọ̀.Òun yóò sì fi ọ̀bẹ ìwẹgi gé àwọ ìsó tuntun kúrò,yóò sì gé àwọn ẹ̀ka tí ó ńgbilẹ̀ lulẹ̀ a sì kó wọn dànù.