Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Maku 7:16-18 BIBELI MIMỌ (BM)

16. Ẹni tí ó bá ní etí láti gbọ́ràn, kí ó gbọ́.”]

17. Nígbà tí ó kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan, tí ó wọ inú ilé lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi í ní ìtumọ̀ òwe yìí.

18. Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin náà kò ní òye? Kò ye yín pé kì í ṣe nǹkan tí ó bá wọ inú eniyan lọ níí sọ eniyan di aláìmọ́?

Ka pipe ipin Maku 7