Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Samuẹli Kinni 23:27-29 BIBELI MIMỌ (BM)

27. Nígbà náà ni oníṣẹ́ kan wá sọ fún Saulu pé, “Pada wá kíákíá, nítorí pé àwọn ará Filistia ti gbógun ti ilẹ̀ wa.”

28. Nítorí náà, Saulu pada lẹ́yìn Dafidi, ó sì lọ bá àwọn ará Filistia jà. Nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni wọ́n ṣe ń pe òkè náà ní Àpáta Àsálà.

29. Láti ibẹ̀, Dafidi lọ farapamọ́ sí Engedi.

Ka pipe ipin Samuẹli Kinni 23