Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Samuẹli Keji 5:6 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí ó yá, Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti ìlú Jerusalẹmu. Àwọn ará Jebusi tí wọn ń gbé ibẹ̀ nígbà náà wí fún Dafidi pé, “O kò lè wọ inú ìlú yìí wá, àwọn afọ́jú ati àwọn arọ lásán ti tó láti lé ọ dànù.” Wọ́n lérò pé Dafidi kò le ṣẹgun ìlú náà.

Ka pipe ipin Samuẹli Keji 5

Wo Samuẹli Keji 5:6 ni o tọ