Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ẹkisodu 20:14-18 BIBELI MIMỌ (BM)

14. “O kò gbọdọ̀ ṣe panṣaga.

15. “O kò gbọdọ̀ jalè.

16. “O kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ọmọnikeji rẹ.

17. “O kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí ilé ọmọnikeji rẹ, tabi sí aya rẹ̀ tabi sí iranṣẹ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, tabi sí akọ mààlúù rẹ̀, tabi sí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, tabi sí ohunkohun tí ó jẹ́ ti ọmọnikeji rẹ.”

18. Nígbà tí àwọn eniyan náà gbọ́ bí ààrá ti ń sán, tí wọ́n rí i bí mànàmáná ti ń kọ, tí wọ́n gbọ́ dídún ìró fèrè, tí wọ́n rí i tí òkè ń rú èéfín, ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì wárìrì. Wọ́n dúró lókèèrè,

Ka pipe ipin Ẹkisodu 20