Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Àwọn Adájọ́ 20:36 BIBELI MIMỌ (BM)

Àwọn ọmọ Bẹnjamini rí i pé wọ́n ti ṣẹgun àwọn. Nígbà tí, àwọn ọmọ Israẹli ṣebí ẹni ń sá lọ fún àwọn ara Bẹnjamini, wọ́n ń tàn wọ́n jáde ni, wọ́n sì ti gbẹ́kẹ̀lé àwọn ará wọn tí wọ́n ba ní ibùba yípo Gibea láti gbógun ti àwọn ará Bẹnjamini.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 20

Wo Àwọn Adájọ́ 20:36 ni o tọ