Róòmù 11:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
Ǹjẹ́ èyí fi hàn wí pé: Ọlọ́run àwọn Júù rẹ ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀ láéláé? Rárá o. Ṣe ni Ọlọ́run ń fi ìgbàlà fún àwọn aláìkọlà. Nípa síṣe bẹ́ẹ̀ yóò mú kí àwọn Júù jowú, kí wọn sì béèrè ìgbàlà Ọlọ́run náà fún ara wọn.