Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà kan, bí ó sì ti ń jẹun pẹ̀lú wọn, ó pàṣẹ yìí fún wọn: “Ẹ má ṣe kúrò ní Jerúsálémù, ṣùgbọ́n ẹ dúró de ẹ̀bùn tí Baba mi se ìlérí, èyí tí ẹ̀yin tí gbọ́ lẹ́nu mi.

Ka pipe ipin Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1

Wo Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1:4 ni o tọ