Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sefanáyà 2:11-13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

11. Olúwa yóò jẹ́ ìbẹ̀rù fún wọn;nígbà tí Òun bá pa gbogbo òrìṣa ilẹ̀ náà run.Orílẹ̀-èdè láti etí odò yóò máa sìn,olúkúlùkù láti ilẹ̀ rẹ̀ wá.

12. “Ẹ̀yin Etiópíà pẹ̀lú,a ó fi idà mi pa yín.”

13. Òun yóò sì na ọwọ́ rẹ̀ sí apá àríwá,yóò sì pa Ásíríà run,yóò sì sọ Nínéfè di ahoro,àti di gbígbẹ bí ihà.

Ka pipe ipin Sefanáyà 2