Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 91:11-15 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

11. Nítorí yóò fi àṣẹ fún àwọn ańgẹ́lì nípa tìrẹláti pa ọ́ mọ ní gbogbo ọ̀nà Rẹ;

12. Wọn yóò gbé ọ sókè ní ọwọ́ wọn,nítorí kí ìwọ má ba à fi ẹsẹ̀ Rẹ̀ gún òkúta.

13. Ìwọ yóò rìn lórí kìnnìún àti paramọ́lẹ̀;ìwọ yóò tẹ kìnnìún ńlá àti ejò nì ìwọ yóò fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀

14. “Nítorí tí ìfẹ́ Rẹ sì mi,”“èmi yóò gbà ọ́;èmi yóò pa ọ́ mọ́, nítorí ìwọ jẹ́wọ́ orúkọ mi.

15. Òun yóò pè mí, èmi yóò sì dáa lóhùn;èmi yóò wà pẹ̀lú Rẹ̀ nínú ipọ́nju,èmi yóò gbà á, èmi yóò sì bu ọlá fún un

Ka pipe ipin Sáàmù 91