Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 136:16-21 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

16. Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn Rẹ̀ la ihà jánítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

17. Fún ẹni tí ó kọ lu àwọn ọba ńlá;nítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

18. Ó sì pa àwọn ọba olókìkínítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

19. Síónì, ọba àwọn ará Ámórìnítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

20. Àti Ógù, ọba Báṣánì;nítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

21. Ó sì fi ilẹ̀ wọn fúnni ní ìní,nítorí tí àánú Rẹ̀ dúró láéláé.

Ka pipe ipin Sáàmù 136