Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 122:7-9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

7. Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi Rẹ̀,àti ire nínú ààfin Rẹ̀.

8. Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mièmi yóò wí nísinsìyí pé,kí àlàáfíà kí ó wà nínú Rẹ̀;

9. Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,èmi yóò máa wá ire Rẹ̀.

Ka pipe ipin Sáàmù 122