Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 120:4-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

4. Òun yóò bá ọ́ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun,pẹ̀lú eyin iná igi ìgbálẹ̀.

5. Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Mésékì,nítorí èmi gbé nínú àgọ́ Kédárì!

6. Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbéláàrin àwọn tí ó kóríra àlàáfíà.

7. Ènìyàn àlàáfíà ni mí;ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ogun ni ti wọn.

Ka pipe ipin Sáàmù 120