Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Sáàmù 109:1-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ọlọ́run, ti èmi ń fi ìyìn fúnMá ṣe dákẹ́

2. Nítorí àwọn ènìyàn búburú àti ẹlẹ́tànti ya ẹnu wọn sí miwọ́n ti fi ahọ́n èké sọ̀rọ̀ sí mi

3. Wọn fi ọ̀rọ̀ ìrira yí mi káàkiri;wọ́n bá mi ja láìnídìí

4. Nípo ifẹ̀ mi, wọn ń ṣe ọ̀tá mi,ṣùgbọ́n èmi ń gba àdúrà.

5. Wọ́n sì fi ibi san ire fún miàti ìríra fún ìfẹ́ mi.

6. Yan àwọn ènìyàn búburú láti dojú kọ ọ́jẹ́ kí àwọn olufisùndúró ní ọwọ́ ọ̀tún Rẹ̀.

Ka pipe ipin Sáàmù 109