Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Oníwàásù 7:26-29 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

26. Mo rí ohun tí ó korò ju ikú lọobìnrin tí ó jẹ́ ẹ̀bìtì,tí ọkàn rẹ̀ jẹ́ tàkútétí ọwọ́ rẹ̀ sì jẹ́ ẹ̀wọ̀n,ọkùnrin tí ó bá tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn yóò le è yọ sílẹ̀ṣùgbọ́n ẹlẹ́ṣẹ̀ kò le è bọ́ nínú tàkúté rẹ̀.

27. Oníwàásù wí pé, “Wò ó” eléyìí ni ohun tí mo ti ṣàwárí:“Mímú ohun kan pọ̀ mọ́ òmíràn láti ṣàwárí ìdí ohun gbogbo.

28. Nígbà tí mo sì ń wá a kiriṣùgbọ́n tí n kò rí ìmo rí ọkùnrin tí ó dúró dáradára kan láàrin ẹgbẹ̀rúnṣùgbọ́n n kò rí obìnrin,kankan kí ó dúró láàrin gbogbo wọn.

29. Eléyìí nìkan ni mo tíì rí:Ọlọ́run dá ìran ènìyàn dáradára,ṣùgbọ́n ènìyàn ti lọ láti ṣàwárí ohun púpọ.”

Ka pipe ipin Oníwàásù 7