Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 9:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Wọ́n sọ fún Mósè pé, “A di aláìmọ́ nípa òkú ènìyàn, ṣùgbọ́n kí ló dé tí a kò fi ní í le è fi ọrẹ wa fún Olúwa pẹ̀lú àwọn ará Ísírẹ́lì yòókù ní àsìkò tí a ti yàn.”

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 9

Wo Nọ́ḿbà 9:7 ni o tọ