“Mó ti fún àwọn ọmọ Léfì ní gbogbo ìdámẹ́wàá ní Ísírẹ́lì gẹ́gẹ́ bí ogún fún iṣẹ́ tí wọ́n ṣe, nígbà tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ níbi àgọ́ ìpàdé