Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Nọ́ḿbà 14:13 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n Mósè sọ fún Olúwa pé, “Nígbà náà ni àwọn ará Éjíbítì yóò gbọ́; Nítorí pé nípa agbára Írẹ ni ìwọ fi mú àwọn ènìyàn wọ̀nyí jáde kúrò láàrin wọn.

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 14

Wo Nọ́ḿbà 14:13 ni o tọ