Náhúmù 1:14 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Nínéfè:“Ìwọ kì yóò ni irú ọmọ láti máa jẹ́ orúkọ rẹ mọ́,Èmi yóò pa ère fínfín àti ère dídà runtí ó wà nínú tẹ́ḿpílì àwọn ọlọ́run rẹ.Èmi yóò wa ibojì rẹ,nítorí ẹ̀gbin ni ìwọ.”