Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóṣúà 19:34-45 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

34. Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Ásínótì, Tabori ó sì jáde ní Húkókì. Ó sì dé Sébúlúnìe ní ìhà gúsù, Ásíẹ́rì ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Jọ́dánì ní ìhà ìlà-oòrùn.

35. Àwọn ìlú olódi sì Sídímù, Sérì, Hámátì, Rákátì, Kínérétì,

36. Ádámà, Rámà Hásórì,

37. Kédéṣì, Édíréì, Ẹ́ní-Hásórì,

38. Írónì, Mígídálì-Élì, Hórémù, Bẹ́tì-Ánátì àti Bẹ́tì-Sẹ́mẹ́ṣì. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.

39. Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Náfitalì, ní agbo ilé sí agbo ilé.

40. Ìbò keje jáde fún ẹ̀yà Dánì, ní agbo ilé ní agbo ilé.

41. Ilẹ̀ ìní wọn nì wọ̀nyí:Sórà, Éṣtaólì, Írí-Ṣẹ́mẹ́sì,

42. Ṣáálábínì, Áíjálónì, Ítílà,

43. Élónì, Tímínà, Ékírónì,

44. Élítékè, Gíbétónì, Báálátì,

45. Jéúdì, Béné-Bérákì, Gátí-Rímónì,

Ka pipe ipin Jóṣúà 19