Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóṣúà 15:48-63 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

48. Ní ilẹ̀ òkè náà:Ṣámírì, Játírì, Sókò,

49. Dánà, Kíríátì-Sánà (tí í se Débírì),

50. Ánábù, Ésítémò, Ánímù,

51. Gósénì, Hólónì àti Gílónì, ìlú mọ́kànlá àti ìletò wọn.

52. Árabù, Dúmà, ṣ Éṣánì,

53. Jánímù, Bẹti-Tápúà, Áfékà,

54. Húmútà, Kíríátì Áríbà (tí í se, Hébúrónì) àti Síori: ìlú mẹ́sàn án àti àwọn ìletò rẹ̀

55. Máónì, Kámẹ́lì, Sífì, Jútà,

56. Jésérẹ́lì, Jókídíámù, Sánóà,

57. Káínì, Gíbíátì àti Tímà: ìlú mẹ́wàá àti àwọn ìletò wọn.

58. Hálíúlì, Bẹti-Súrì, Gédórì,

59. Máárátì, Bẹti-Ánótì àti Élítékónì: ìlú mẹ́fà àti àwọn ìletò wọn.

60. Kiriati Báálì (tí í ṣe, Kiriati Jeárímù) àti Rábà ìlú méjì àti ìletò wọn.

61. Ní asálẹ̀:Bẹti-Árábà, Mídínì, Sékákà,

62. Níbíṣánì, Ìlú Iyọ̀ àti Ẹni-Gẹ́dì, ìlú mẹ́fà àti ìletò wọn.

63. Júdà kò lè lé àwọn ọmọ Jébúsì jáde, tí wọ́n ń gbé ní Jérúsálẹ́mù. Àwọn ará Jébúsì sì ń gbé pẹ̀lú àwọn ènìyàn Júdà títí dí òní.

Ka pipe ipin Jóṣúà 15