Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóṣúà 15:40-57 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

40. Kábónì, Lámásì, Kítílísì,

41. Gédérótì, Bẹti-Dágónì, Náámà àti Mákédà, ìlú mẹ́rìndín ní ogún àti ìletò wọn.

42. Líbínà, Étíérì, Áṣánì,

43. Hífítà, Ásínà, Nésíbù,

44. Kéílà, Ákísíbì àti Máréṣà, ìlú mẹ́sàn àti àwọn ìletò wọn. (9)

45. Ékírónì, pẹ̀lú ibùgbé àti àwọn ìletò rẹ̀ tó yí i ká,

46. ìwọ̀-oòrùn Ékírónì, gbogbo èyí tí ń bẹ nítòòsí Áṣídódù, pẹ̀lú àwọn ìletò wọn,

47. Áṣídódù, agbégbé ìlú rẹ̀ àti ìletò; àti Gásà, ìlú rẹ̀ àti ìletò, títí ó fi dé Wádì ti Éjíbítì àti agbégbé òkun ńlá (òkun Mẹditareníà).

48. Ní ilẹ̀ òkè náà:Ṣámírì, Játírì, Sókò,

49. Dánà, Kíríátì-Sánà (tí í se Débírì),

50. Ánábù, Ésítémò, Ánímù,

51. Gósénì, Hólónì àti Gílónì, ìlú mọ́kànlá àti ìletò wọn.

52. Árabù, Dúmà, ṣ Éṣánì,

53. Jánímù, Bẹti-Tápúà, Áfékà,

54. Húmútà, Kíríátì Áríbà (tí í se, Hébúrónì) àti Síori: ìlú mẹ́sàn án àti àwọn ìletò rẹ̀

55. Máónì, Kámẹ́lì, Sífì, Jútà,

56. Jésérẹ́lì, Jókídíámù, Sánóà,

57. Káínì, Gíbíátì àti Tímà: ìlú mẹ́wàá àti àwọn ìletò wọn.

Ka pipe ipin Jóṣúà 15