Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóṣúà 15:30-45 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

30. Elitóládì, a Késílì, Hórímà,

31. Síkílágì, Mádímánà, Sánsánà,

32. Lébáótì, Sílímù, Háínì àti Rímónì, àpapọ̀ ìlú mọ́kàndín ní ọgbọ̀n àti àwọn ìlétò wọn.

33. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹsẹ̀ òkè:Ésítaólì, Sórà, Áṣínà,

34. Sánóà, Eni-Gánímù, Tápúà, Énámù,

35. Jámútì, Ádúlámù, Sókò, Ásekà,

36. Ṣááráímù, Ádítaímù àti Gédérà (tàbí Gérérótíámù), ìlú mẹ́rìnlá àti àwọn ìletò wọn.

37. Sénánì, Hádáṣà, Mígídánì-Gádì,

38. Díléánì, Mísípà, Jókítẹ́lì,

39. Lákísì, Bósíkátì, Égílónì,

40. Kábónì, Lámásì, Kítílísì,

41. Gédérótì, Bẹti-Dágónì, Náámà àti Mákédà, ìlú mẹ́rìndín ní ogún àti ìletò wọn.

42. Líbínà, Étíérì, Áṣánì,

43. Hífítà, Ásínà, Nésíbù,

44. Kéílà, Ákísíbì àti Máréṣà, ìlú mẹ́sàn àti àwọn ìletò wọn. (9)

45. Ékírónì, pẹ̀lú ibùgbé àti àwọn ìletò rẹ̀ tó yí i ká,

Ka pipe ipin Jóṣúà 15