Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóṣúà 15:20-27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

20. Èyí ni ilẹ̀ ini ẹ̀yà àwọn ọmọ Júdà gẹ́gẹ́ bi ìdílé wọn.

21. Ìlú ìpẹ̀kun gúsù ti ẹ̀yà Júdà ní Négéfi ní ààlà Édómù niwọ̀nyí:Kabísélì, Édérì, Jágúrì,

22. Kínà, Dímónà, Ádádà,

23. Kédéṣì, Hásórì, Ítina,

24. Sífì, Télémù, Bíálótì,

25. Hasori-Hádátà, Kerioti-Hésírónì (tí í ṣe Hásórì),

26. Ámámù, Sẹ́mà, Móládà,

27. Hasa-Gádà, Hésímónì, Bẹti-Pélétì,

Ka pipe ipin Jóṣúà 15