Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóòbù 36:29-33 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

29. Pẹ̀lúpẹ̀lú ẹnikẹ́ni lè imọ́ ìtànkáàwọ̀sánmọ̀, tàbí ariwo àrá láti àgọ́ rẹ̀?

30. Kíyèsí i, ó tan ìmọ́lẹ̀ yí ara rẹ̀ká ó sì bo ìsàlẹ̀ òkun mọ́lẹ̀.

31. Nitorí pé nípa wọn ní ń ṣe dájọ́àwọn orílè èdè ènìyàn; ó sí ń pèsè oúnjẹ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.

32. Ó fi ìmọ́lẹ̀ bo ọwọ́ rẹ̀ méjèèje ó sìrán sí ẹni olódì.

33. Ariwo àrá rẹ̀ fi ìjì hàn ní; ọ̀wọ́ẹran pẹ̀lú wí pé, ó súnmọ́ etílé!

Ka pipe ipin Jóòbù 36