Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jóòbù 21:10-17 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

10. Akọ màlúù wọn a máa gùn, kì ísìíṣe; abo màlúù wọn a máa bí, kì í sì í ṣẹ́yun;

11. Wọn a máa rán àwọn ọmọ wọnwẹ́ẹ́wẹ́ẹ́ jáde bí agbo ẹran, àwọn ọmọ wọn a sì máa jó kiri.

12. Wọ́n mú ohun ọ̀nà orin, ìlù àtiháápù, wọ́n sì ń yọ̀ sí ohùn fèrè

13. Wọ́n ní ọjọ́ wọn nínú ọrọ̀; wọnsì lọ sí ipò òkú ní àlàáfíà.

14. Nítorí náà ni wọ́n ṣe wí fúnỌlọ́run pé, lọ kúrò lọ́dọ̀ wa,nítorí pé wọn kò fẹ́ ìmọ̀ ipa ọ̀nà rẹ!

15. Kí ni Olódùmarè tí àwa ó fi máasìn in? Èrè kí ni a ó sì jẹ bí àwa ba gbàdúrà sí i?

16. Kíyè sí i, àlàáfíà wọn kò sí nípaọwọ́ wọn; ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà sí ni réré.

17. “Ìgbà mélòómélòó ní a ń pa iná ènìyànbúburú kú? Ìgbà mélòómélòó ní ìparunwọn dé bá wọn, tí Ọlọ́run sì ímáa pín ìbìnújẹ́ nínú ìbínú rẹ̀?

Ka pipe ipin Jóòbù 21