Jeremáyà 20:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
Mo gbọ́ sísọ ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́,ìbẹ̀rù ni ibi gbogboFi í sùn! Jẹ́ kí a fi sùn!Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ mi ń dúrókí èmi ṣubú, wọ́n sì ń sọ pé,Bóyá yóò jẹ́ di títàn,nígbà náà ni àwa yóò borí rẹ̀,àwa yóò sì gba ẹ̀san wa lára rẹ̀.”