Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Jeremáyà 10:20-24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

20. Àgọ́ mi bàjẹ́, gbogbo okùn rẹ̀ sì já.Àwọn ọmọ mi ti lọ lọ́dọ̀ mi, wọn kò sì sí mọ́Kò sí ẹnìkankan pẹ̀lú mi mọ́, báyìí kò sí ẹni tí yóòná àgọ́ mi tàbí ṣe ibùgbé fún mi

21. Àwọn olùsọ́ àgùntàn jẹ́ aláìlóye, wọnkò sì wá Olúwa: nítorí náà wọn kì yóòṣe rere àti pé gbogbo agbo wọn ni yóò túká.

22. Fetísílẹ̀; ariwo ìdàrúdàpọ̀ ńlá náà ń bọ̀láti ilẹ̀ àríwá, yóò sì sọ ìlú Júdà diahoro àti ihò jàkùmọ̀

23. Èmi mọ̀ Olúwa wí pé ayé ènìyàn kì íṣe ti ara rẹ̀, kì í ṣe fún ènìyàn láti gbe igbésẹ ara rẹ̀.

24. Tún mi ṣe Olúwa, pẹ̀lú ìdájọ́ nìkankí o má sì ṣe é nínú ìbínú rẹ. Kí ìwọmá ṣe sọ mí di òfo.

Ka pipe ipin Jeremáyà 10