“Ọmọ ènìyàn, èmi fi ọ ṣe alóre fún ilé Ísírẹ́lì; nítorí náà gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo sọ, kí o sì fún wọn ni ìkìlọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.