“Ọmọ ènìyàn; sọ fún ilé Ísírẹ́lì, ‘Èyí yìí ní ìwọ sọ: “Àwọn ìrékọjá àti ẹ̀ṣẹ̀ wa tẹ orí wa ba, àwa sì ń sòfò dànù nítorí wọn. Bá wó wa ni a ṣe lè yè?” ’