Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ísíkẹ́lì 31:5-10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Nítorí náà ó ga sí òkè fíofíoju gbogbo igi orí pápá lọ;Ẹ̀ka rẹ̀ pọ̀ sí i:àwọn ẹ̀ka rẹ̀ sì gùn,wọn tẹ́ rẹrẹ nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi.

6. ẹyẹ ojú ọ̀runkọ ilé sí ẹ̀ka rẹ̀gbogbo ẹranko ìgbẹ́ń bímọ ní abẹ́ ẹ̀ka rẹ̀;gbogbo orílẹ̀ èdè ńláń gbé abẹ́ ìjì rẹ̀.

7. Ọlá ńlá ní ẹwà rẹ̀ jẹ́,pẹ̀lú títẹ́ rẹrẹ ẹ̀ka rẹ̀,nítorí gbòǹgbò rẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀sí ibi tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi wà.

8. Àwọn òpépé igi nínú ọgbà Ọlọ́runkò lè è bá a dọ́gba,tàbí kí àwọn igi firiṣe déédé pẹ̀lú ẹ̀ka rẹ̀,tàbí kí a fi igi títẹ́ rẹrẹ wé ẹ̀ka rẹ̀,kò sí igi nínú ọgbà Ọlọ́runtí ẹwà rẹ̀ ṣe déédé pẹ̀lú rẹ̀.

9. Mo mú kí ó ní ẹwàpẹ̀lú ẹ̀ka lọ́pọ̀lọpọ̀tó fi jẹ́ ìlara àwọn igi gbogbo ní Édẹ́nìtí í ṣe ọgbà Ọlọ́run.

10. “ ‘Nítorí náà, èyí yìí ńi Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí; Nítorí pé ó ga lọ sókè fíofío, tí ó sì gbé òkè rẹ̀ ga ju ewé tí ó nípọn kọ́, àti nítorí pé gíga rẹ mú kí ó gbéraga,

Ka pipe ipin Ísíkẹ́lì 31