Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Ísíkẹ́lì 15:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run wí: Bí mo ṣe sọ igi àjàrà tó wà láàrin àwọn igi inú igbó yóòkù di igi ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe ṣe gbogbo ènìyàn tó ń gbé Jérúsálẹ́mù.

Ka pipe ipin Ísíkẹ́lì 15

Wo Ísíkẹ́lì 15:6 ni o tọ