Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Hósíà 7:5-12 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Ní ọjọ́ àjọ̀dún ọba wawáìnì mú ara àwọn ọmọ aládé gbónáó sì darapọ̀ mọ́ àwọn oníyẹ̀yẹ́.

6. Ọkàn wọn ń gbóná bí i ààròwọ́n sì tọ̀ ọ́ lọ pẹ̀lú rìkísí,ìbínú wọn pa lọ́lọ́ ní gbogbo òruó sì bú jáde bí ọ̀wọ́ iná ní òwúrọ̀.

7. Gbogbo wọn gbóná bí ààròwọ́n pa gbogbo olórí wọn run,gbogbo ọba wọn si ṣubúkò sì sí ẹnìkan nínú wọn tí ó ké pè mí.

8. “Éfúráímù ti darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn náà;Éfúráímù jẹ́ àkàrà tí a kò yípadà

9. Àwọn àlejò ti jẹ agbára rẹ̀ runṣùgbọ́n kò sì mọ̀,Ewú ti wà ní orí rẹ̀ káàkiribẹ́ẹ̀ ni kò kíyèsíi

10. Ìgbéraga Ísírẹ́lì ń jẹ́rìí sí iṣùgbọ́n pẹ̀lú gbogbo èyíkò padà sí ọ̀dọ̀ OlúwaỌlọ́run, tàbí kí ó wá a.

11. “Éfúráímù dàbí àdàbàtó rọrùn láti tàn jẹ àti aláìgbọ́ntó wá ń pé Éjíbítì nísinsìn yìító sì tún ń padà lọ si Ásíríà.

12. Nígbà tí wọ́n bá lọ, èmi ó ta àwọ̀n mi sórí wọnÈmi ó fà wọ́n lulẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ ojú ọ̀runNígbà tí mo bá gbọ́ pé wọ́n rìn pọ̀Èmi nà wọ́n bí ìjọ ènìyàn wọn ti gbọ́

Ka pipe ipin Hósíà 7