Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Hósíà 11:1-5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. “Nígbà tí Ísírẹ́lì wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀,mo sì pe ọmọ mi jáde wá láti Éjíbítì.

2. Wọ́n rúbọ sí Báálì bí mo ṣe ń pe Ísírẹ́lì síbẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń sá kúrò lọ́dọ̀mi jìnnà sí i: wọn rúbọ sí báálímu,wọn sì fi tùràrí jóná sí ère fínfín.

3. Lóòtọ́ mo kọ́ Éfúráímù pẹ̀lú ní ìrìnmo di wọ́n mú ní apá,ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀pé mo ti mú wọn lára dá.

4. Mo fó okùn ènìyàn fà wọ́nàti ìdè ìfẹ́.Mo mú àjàgà kúrò ni ọrùn wọnMo sì farabalẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.

5. “Ṣé wọn ò wá ní padà sí Éjíbítì bíṢé Ásíríà kò sì ní jẹ ọba lé wọn lórí bínítorí pé wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronú pìwàdà?

Ka pipe ipin Hósíà 11