Ékísódù 4:30-31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)
30. Árónì sọ ohun gbogbo tí Olúwa sọ fún Mósè fún wọn
31. Wọ́n sì gbàgbọ́. Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé Olúwa ti bẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì wò àti pé Olúwa ti gbọ́ nípa ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sì sìn ín. Ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ amì náà níwájú àwọn ènìyàn náà.