Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Dáníẹ́lì 11:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Nígbà náà ni ọba Gúṣù yóò jáde pẹ̀lú ìbínú, yóò sì bá ọba àríwá jà, ẹni tí yóò kó ọmọ ogun púpọ̀ jọ, ṣùgbọ́n ọba Gúṣù yóò borí i wọn.

Ka pipe ipin Dáníẹ́lì 11

Wo Dáníẹ́lì 11:11 ni o tọ