17. Ṣébàdíáhì, Mésúlámù Hésékì, Hébérì
18. Íṣíméráì, Íṣílíáhì àti Jóbábì jẹ́ àwọn ọmọ Élípálì.
19. Jákímì, Ṣíkírì, Ṣábídì,
20. Élíénáì Ṣílétaì Élíélì,
21. Ádáyà, Béráíáhì àti Ṣímírátì jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣíméhì.
22. Íṣípánì Ébérì, Élíélì,
23. Ábídónì, Ṣíkírì, Hánánì,
24. Hánáníyà, Élámù, Ánítótíjáhì,
25. Ífédíà Pénúélì jẹ́ àwọn ọmọ Ṣásákì.
26. Ṣámíséráì, Ṣéháríà, Átalíà
27. Járéṣíà Élíjà àti Ṣíkírì jẹ́ àwọn ọmọ Jéróhámù.
28. Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ó lẹ́sẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jérúsálẹ́mù.
29. Jélíélì, baba a Gíbíónì ń gbé ní Gíbíónì.Ìyáwó o Rẹ̀ a má jẹ́ Mákà,
30. Àkọ́bí Rẹ̀ a sì má a jẹ́ Ábídónì wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Ṣúrì, Kíṣì, Báláhì, Nérì, Nádábù,