Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

1 Kíróníkà 6:7-22 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

7. Méráíótì baba Ámáríyà,Ámáríyà baba Áhítúbì

8. Álítúbù bàbá Ṣádókù,Ṣádókù baba Áhímásì,

9. Áhímásì baba Áṣáríyà,Ásáríyà baba Jóhánánì,

10. Jóhánánì baba Áṣáríyà (Òhun ni ó sìn gẹ́gẹ́ bí àlùfáà nínú ilé Olúwa tí Sólómónì kọ́ sí Jérúsálẹ́mù),

11. Áṣáríyà baba ÁmáríyàÁmáríyà baba Áhítúbì

12. Áhítúbì baba Ṣádókù.Ṣádókù baba Ṣálúmù,

13. Ṣálúmù baba Hílíkíyà,Hílíkíyà baba Áṣáríyà,

14. Áṣáríyà baba Ṣéráíà,pẹ̀lú Ṣéráíà baba Jéhósádákì

15. A kó Jéhósádákì lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Júdà àti Jérúsálẹ́mù kúrò ní ìlú nípaṣẹ̀ Nebukadinésárì.

16. Àwọn ọmọ Léfì:Gérísónì, kóhátì àti Mérárì.

17. Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Géríṣónì:Líbínì àti Ṣíméhì.

18. Àwọn ọmọ Kéhátì:Ámírámù, Íṣárì, Hébírónì àti Húsíélì.

19. Àwọn ọmọ Mérárì:Máhílì àti Múṣì.Wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ará Léfì tí a kọ ní ṣíṣẹ̀ ń tẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí baba wọn:

20. Ti Gérísómù:Líbínì ọmọkùnrin Rẹ̀, JéhátìỌmọkùnrin Rẹ̀, Ṣímà ọmọkùnrin Rẹ̀,

21. Jóáhì ọmọkùnrin Rẹ̀,Idò ọmọkùnrin Rẹ̀, Ṣéráhì ọmọkùnrin Rẹ̀àti Jéátéráì ọmọkùnrin Rẹ̀.

22. Àwọn ìran ọmọ Kóhátì:Ámínádábù ọmọkùnrin Rẹ̀, Kóráhì ọmọkùnrin Rẹ̀,Ásírì ọmọkùnrin Rẹ̀.

Ka pipe ipin 1 Kíróníkà 6