Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

1 Kíróníkà 6:15-27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

15. A kó Jéhósádákì lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Júdà àti Jérúsálẹ́mù kúrò ní ìlú nípaṣẹ̀ Nebukadinésárì.

16. Àwọn ọmọ Léfì:Gérísónì, kóhátì àti Mérárì.

17. Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Géríṣónì:Líbínì àti Ṣíméhì.

18. Àwọn ọmọ Kéhátì:Ámírámù, Íṣárì, Hébírónì àti Húsíélì.

19. Àwọn ọmọ Mérárì:Máhílì àti Múṣì.Wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ará Léfì tí a kọ ní ṣíṣẹ̀ ń tẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí baba wọn:

20. Ti Gérísómù:Líbínì ọmọkùnrin Rẹ̀, JéhátìỌmọkùnrin Rẹ̀, Ṣímà ọmọkùnrin Rẹ̀,

21. Jóáhì ọmọkùnrin Rẹ̀,Idò ọmọkùnrin Rẹ̀, Ṣéráhì ọmọkùnrin Rẹ̀àti Jéátéráì ọmọkùnrin Rẹ̀.

22. Àwọn ìran ọmọ Kóhátì:Ámínádábù ọmọkùnrin Rẹ̀, Kóráhì ọmọkùnrin Rẹ̀,Ásírì ọmọkùnrin Rẹ̀.

23. Élikánà ọmọkùnrin Rẹ̀,Ébíásáfí ọmọkùnrin Rẹ̀,Ásírì ọmọkùnrin Rẹ̀.

24. Táhátì ọmọkùnrin Rẹ̀, Úríélì ọmọkùnrin Rẹ̀,Úsíáhì ọmọkùnrin Rẹ̀ àti Ṣọ́ọ̀lù ọmọkùnrin Rẹ̀.

25. Àwọn ìran ọmọ Élíkánáhì:Ámásáyì, Áhímótì

26. Élíkáná ọmọ Rẹ̀, Ṣófáì ọmọ Rẹ̀Náhátì ọmọ Rẹ̀,

27. Élíábù ọmọ Rẹ̀,Jéríhámù ọmọ Rẹ̀, Élíkáná ọmọ Rẹ̀àti Ṣámúẹ́lì ọmọ Rẹ̀.

Ka pipe ipin 1 Kíróníkà 6