Atijọ Majemu

Majẹmu Titun

Luku 11:24 BIBELI MIMỌ (BM)

“Nígbà tí ẹ̀mí èṣù bá jáde kúrò ninu ẹnìkan, á máa wá ilẹ̀ gbígbẹ kiri láti sinmi. Nígbà tí kò bá rí, á ní, ‘N óo tún pada sí ilé mi níbi tí mo ti jáde kúrò.’

Ka pipe ipin Luku 11

Wo Luku 11:24 ni o tọ